YEPARIPA!!! ERÍNWÓ, ẸJA NLA LỌ LÓMI: CHINUA ACHEBE, THE TITAN HAS FALLEN

Ìròyìn ikú Olõgbe Chinua Achebe, ògúnná gbongbo ninu Olukọwe ilẹ̀ aláwọ̀ dúdú àti àgbáyé kàn ni ọjọ́ Ẹtì, ọjọ́ kejì lélógún, oṣ̀u kẹta ọdún ẹgbẹ̀rún meji le mẹ́tàlá.  Ọmọ ọdún meji le lọgọrin ni Olõgbe Chinua Achebe nígbà ti o pa ipòdà.

Ìkan nínú ìwé ti Olõgbe Chinua Achebe kọ “Nkan túká” di kíkà fún àwọn ọmọ ilé-ìwé lati ilẹ̀ ènìà dúdú títí dé Òkè-òkun/ìlú-òyìnbó.  Títí di àsìkò yi, ìwé na ngbayi si ni, nítorí wọn ti túmọ̀ ìwé yi sí èdè oriṣiriṣi.

Àdánù nla ni ikú Olõgbe Chinua Achebe jẹ́ fún Naijeria, ìlú aláwọ dúdú àti gbogbo Olùkọ̀wé lagbaye.

Sunre o, Ologbe Chinua Achebe.

The news of the death of Late Chinua Achebe, a Prominent Writer in Africa and Literature giant in the World was announced on Friday, 22nd March, 2013.  He was 82 years old at the time of transition.

One of the Literature Books written by Chinua Achebe “Things Fall Apart” is being read by students in many African Countries and Abroad/Europe as it has been translated to several languages and it continues to be in demand.

Chinua Achebe’s death is a big loss not only for Nigeria but Africa and all Writers in the World.

Sleep on Late Chinua Achebe.

Share Button

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

Time limit is exhausted. Please reload the CAPTCHA.