Tag Archives: Parental roles

“Ọmọdé ò jobì, àgbà ò jẹ oyè” Èrè Òbí tó kọ ọmọ sílẹ̀: The consequence for parents that neglect their children

Yorùbá ni “Ọmọdé ò jobì, àgbà ò jẹ oye”, òwe yi bá àwọn òbí ti ó kọ ọmọ sílẹ̀, ìyá ti ó ta ọmọ, bàbá ti ó sá fi ọmọ sílẹ̀ àti àwọn ti o fi ìyà jẹ ọmọ, irú ọ̀pọ̀lọpọ̀ òbí bayi ni òṣì má ta pa.  Kò sí àyè fún ọmọ irú àwọn bayi lati mọ wọn lójú nítorí wọn o si nílé lati ṣe ojuṣe wọn gẹ́gẹ́bí òbi ati lati kọ́ ọmọ aláìgbọràn.   Irú orin bayi ló tọ́ sí irú òbí bẹ̃:

MP3 Below:

Download: Ise obi fun omo – Parental responsibilities

Íya tó kọ̀ ọ̀mọ̀ rẹ sílẹẹ̀

Oṣí yo tà yà na paá

Bába tó kọ̀ ọ̀mọ rẹ́ silẹ̀

Oṣí yo tà bà nà paá

Ìyà tò fiyà jọmọ́ r

Bàbà tò fiyà jọmọ́ r

Íya tó kọ̀ ọ̀mọ̀ rẹ sílẹẹ̀

Oṣí yo tà yà na paá

Bába tó kọ̀ ọ̀mọ rẹ́ silẹ̀

Oṣí yo tà bà nà paá

ENGLISH TRANSLATION

According to the “Yoruba Proverbs” by Oyekan Owomoyela’s translation, “The youth does not eat kola nuts; the elder does not win the chieftaincy title” meaning (If you do not cultivate others, even those lesser than yourself, then you cannot expect any consideration from them).  This is apt to describe the consequence for a mother that sells her child, a father that abandon his children and those abusing their children.  Many children has no privilege of seeing their parents when they are young let alone disobey or refuse correction, hence such parents would be the ones to suffer poverty in the end.  The song below is for parents that have abandoned their role:

Mother that abandoned her child

Will suffer poverty in the end

Father that abandoned his child

Will suffer poverty in the end

Mother that abuses her child

Father that abuses his child

Mother that abandoned her child

Will suffer poverty in the end

Father that abandoned his child

Will suffer poverty in the end

Share Button

Originally posted 2013-07-26 20:30:36. Republished by Blog Post Promoter