Tag Archives: Obafemi Awolowo

“Orin ẹ̀kọ́ lati bọ̀wọ̀ fún òbí ni ilé-ìwé alakọbẹrẹ”: Primary School song to teach respect for parents

Orin yi ni Olùkọ́ ma fi ńkọ́ àwọn ọmọ ilé-ìwé alakọbẹrẹ nigbà “ilé-ìwé ọ̀fẹ́” ti àwọn Òṣèlú ilẹ̀ Yorùbá ti Olóyè Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ ṣe olórí rẹ.  Ni ayé ìgbà wọnyi, ọ̀pọ̀lọpọ̀ òbí a ma fi ebi panú, ṣiṣẹ́ kárakára tàbí ta ohun ìní lati pèsè fún àwọn ọmọ àti lati rán ọmọ lọ sí ilé-ìwé gíga.  O yẹ ki ọmọ bọ̀wọ̀ fún irú àwọn òbí wọnyi.

MP3 Below

Download: Omo to moya iya loju – Respect for parents

Ọ́mọ tó mọ̀ yà rẹ lóju ò                                                

Oṣí yo tá mọ náà pàa                                   

Ọ́mọ tó mọ̀ bà rẹ lóju o                               

Oṣí yo tá mọ náà pàa                                   

Iyà rẹ̀ jiyà pọ̀ lorí rẹ                              

Bàbà rẹ̀ jiya pọ̀ lorí rẹ                          

Ọ́mọ tó mọ̀ yà rẹ lóju ò                

Oṣí yo tá mọ náà pàa

Ọ́mọ tó mọ̀ bà rẹ lóju o

Oṣí yo tá mọ náà pàa

ENGLISH TRANSLATION

During the “Free Education Programme in the Western State of Nigeria” that was created by the Politicians led by Chief Obafemi Awolowo, Primary School pupils are thought the song below to teach respect for parents.  At that period, many parents denied themselves of food, worked hard or even sell their properties in order to provide for their children and to educate them in the Higher Institutions.  It is only apt for such children to respect such parents.

The child that disobey his/her parent

Will suffer poverty in the end

The child that disobey his/her father

Will suffer poverty in the end

Your mother suffered so much for you

Your father suffered so much for you

A child that disobey his/her parent

Will suffer poverty in the end

A child that disobey his/her father

Will suffer poverty in the end

 

 

Share Button

Originally posted 2013-07-26 20:21:43. Republished by Blog Post Promoter