Tag Archives: News

Bί a bá ránni ni iṣẹ ẹrú: One sent on a slavish errand (on man’s inhumanity to man)


The Mido Macia Story courtesy of NEWSY reporting from multiple sources and giving a broader view


Yorὺbá nί “Bί a bá ránni nί iṣẹ ẹrú, a fi tọmọ jẹ”.  Ọlọpa tί o yẹ ki o dãbo bo ará àti ẹrú nί ìlú, nhuwa ìkà sί àwọn tί o yẹ ki wọn ṣọ.  Ọlọpa South Africa so ọdọmọkunrin ọmọ ọdún mẹta dinlọgbọn – Mido Gracia, mọ ọk`ọ ọlọpa, wọ larin ìgboro, lu, lẹhin gbogbo eleyi, ju si àtìm`ọle tίtί o fi kú.  Ọlọpa wọnyi hὺ ìwà ìkà yί nίgbangba lai bìkίtà pe aye ti lujára. Eleyi fi “Ìwà ìkà ọmọ enia sί ọmọ enia han”.   Ọlọpa South Africa ṣi àṣẹ ti wọn nί lὸ, wọn rán wọn niṣe ẹrú, wọn o fi tọmọ jẹ.  Sὺnre o Mido Macia.

ENGLISH TRANSLATION

Yoruba proverb says that, “One sent on a slavish errand, should deliver the message with the discretion of an heir”. Continue reading

Share Button

Originally posted 2013-03-02 00:25:30. Republished by Blog Post Promoter

“Ẹrú kan ló mú ni bú igba ẹrú”: “One slave causes the abuse of two hundred others”.

Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Yorùbá ló nṣe dáradára ní ilé àti àjò tí a kò gbọ́ ìròyìn wọn.  Óṣeni lãnu wípé àwọn diẹ tó nṣe iṣẹ́ ibi bi: gbígbé oògùn olóró, ẹgbẹ́ òkùnkùn, olè jíjà àti bẹ̃bẹ lọ mba àwọn yoku jẹ.

Yorùbá ni “Ẹni jalè ló bọmọ jẹ”, ìròyìn iṣẹ́ rere ki tàn bi irú ìròyìn iṣẹ ibi ti Michael Adébọ́lájọ àti Michael Adé́bọ̀wálé tó kárí ayé.

Ó yẹ ki Ìjọba àti gbogbo Yorùbá pa ẹnu pọ lati bá oníṣẹ ibi wi nítorí gẹ́gẹ́bí òwe Yorùbá “Ẹrú kan ló́ mú ni bu igba ẹrú”.

ENGLISH TRANSLATION

Many Yoruba indigenes that are doing well both at home and abroad never made any news.  It is unfortunate that the few that engaged in evil acts like: drug peddling, cultism, stealing etc. are destroying the good work of the others.

Yoruba adage said “He/She who steals destroys the innocence of a child”, news about good deed never spread like the news of the recent evil act committed by the duo: Michael Adebolajo and Michael Adebowale that spread all over the world.

It is apt for the Government and all Yoruba indigenes to join hands to condemn evil because according to the Yoruba proverb, “One slave causes the abuse of two hundred”.

Share Button

ÌRÒYÌN – NEWS: Ogun àsọ tẹlẹ – A War Aforetold

ÌRÒYÌN ÌJÌ NLA JÀ NI ÌBÀDÀN: NEWS OF RAIN STORM IN THE IBADAN

Òjò ati ìjì bẹrẹ ni arọkutu ọjọ ajé, ọjọ kejidinlogun oṣu keji ọdún ẹgbẹwa le mẹtala.  Ìjì naa ba ílé ati ọna jẹ rẹpẹtẹ ni ìlú Ìbàdàn

Òwe Yorùbá sọ wipe “Ogun àsọ tẹlẹ ki parọ to ba gbọn”.  O ṣeni lanu wipe ko si àsọ tẹl tabi ipalẹmọ fún ará ìlú ati ijọba.  Iyalẹnu ni wipe lati ọpọ ọdun ti ìjì àti àgbàrá lati odò Ògùnpa ti mba ilé ati ọna jẹ lọdọdun, Ìjọba Ọyọ ko ti ri ogbọn kọ lati da ẹkun ati ibanujẹ ti iṣẹlẹ yi nda silẹ.

ENGLISH TRANSLATION

Rain storm began early on Monday morning, 18 February, 2013.  The rain storm destroyed homes and properties in Ogun state, Nigeria. Continue reading

Share Button